Business

N I G E R I A

Africa In Miniature

World News in Yoruba


From The BBC

Yèyé Osun, babaláwo àti alfa tó ń ṣe alápatà ẹran èèyàn kó sí gbaga ọlọ́pàá
Ademola Akinlosotu to jẹ olori awọn afurasi naa ni alukoro ọlọpaa ni o jẹwọ pe niṣe loun maa n hu oku awọn eeyan kaakiri ibi-isinku ti oun yoo si ta ẹya ara wọn fawọn to n ṣe oogun owo.


Kí ni àjọṣepọ̀ tó wà láàrín Iyemọja, Ẹ̀fẹ̀ àti Gẹ̀lẹ̀dẹ́ tó fi di òun tí gbogbo àgbàyé ń pé wò nílùú Ibara
Ọdun mẹtamẹta ni ajọdun naa maa n waye.


Ilé alájà márùn ún dàwó, gbẹ̀mí èèyàn mẹ́rin
Aadọta eeyan lo ha si abẹ awoku ile alaja marun un naa.


Àwọn àǹfàní àti àléébù wo ló wà nínú fífi owó kún owó òṣìṣẹ́?
Pẹ̀lú bí àwọn nǹkan ṣe ń gbówó lórí yìí, àwọn onímọ̀ sọ pé ìjọba nílò láti rí pé wọ́n pèsè àwọn ohun amáyédẹrùn kan kí owó tí wọ́n bá máa fi kún owó òṣìṣẹ́ le ní ìtumọ̀.


Hamas ṣetán láti dáwọ́ ogun dúró lẹ́yìn tí Israel pinnu láti ṣe ìkọlù sí ìlú Rafah
Netanyahu ni ko si ohun ti yoo yẹ ikọlu naa bo tilẹ jẹ pe ọrọ ajọsọ lati lati dawo ogun duro n waye laarin rẹ ati ẹgbẹ ọmọ ogun Hamas.


Wo ìdí tí ẹni tí ipò Olubadan kàn fi ṣàbẹ̀wò sílé Olubadan àná
Osi Balogun ṣalaye pe igba akọkọ ree ti ẹni ti oye Olubadan kan yoo ṣe abẹwo si ile Olubadan to gbeṣe niluu Ibadan.


Àwọn nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ètò ìdìbò ààrẹ tó bẹ̀rẹ̀ ní Chad
Olùdíje ogún ló fi ìwé ẹ̀rí wọn kalẹ̀ síwájú ìgbìmọ̀ tó ń rí sí ètò ìdìbò èyí tó wáyé láàárín ọjọ́ Kẹfà sí ọjọ́ Kẹẹ̀dógún, oṣù Kẹta fún àyẹ̀wò.


Iléeṣẹ́ iná mọ́nàmọ́ná kéde àdínkù owó ìná ẹ̀lẹ́ńtíríkì
Ọpọlọpọ ariwo lo ti n waye lori afikun owo ina mọnamọna ti ijọba apapọ orilẹede Naijiria kede loṣu diẹ sẹyin.


Awuyewuye lórí ìgbéyàwó Taiwo Cole, ìyàwó Wofai ní òòyà ò le ya àwọn, ẹbí ọkọ 'fàáké kọ́rí'
Lẹyin ti fọto igbeyawo Taiwo ati Wofai lu ori ayelujara pa tan lọjọ Aiku ọjọ karun un oṣu Karun un ni ẹbi Cole fi atẹjade kan sita ninu eyi ti wọn ti sọ pe awọn ko fọwọ si igbeyawo laarin awọn mejeeji.


Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ṣàlàyé ìdí tó fi fẹ́ wó ọgọ́rùn-ún ilé abẹ́ afárá Adeniji Adele lónìí
Kọmiṣọna fun ọrọ eto ayika ati alumọni inu omi nipinlẹ Eko, Tokunbo Wahab lo fọrọ yii lede loju opo X rẹ.


Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo tẹ babaláwo àtàwọn tó ń fi ẹ̀yà ara èèyàn gún ọṣẹ
Lasiko to n awọn akọroyin sọrọ, babalawo Quadri Lawal sọ pe wọn ma n lo eya ara awọn eniyan lati fi gun ọsẹ fun awọn to ba nilo rẹ, to si jẹ pe eya ara ti awọn onibara wọn ba bere fun lawọn ma n wa kiri.


Afurasí tó máa ń jí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ nílé ìjọsìn kó sí gbaga ọlọ́pàá Ekiti
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin.


Ṣé lóòtọ́ọ́ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Eko dá àwọn olùgbé ìlú Eko kan padà sí ìpínlẹ̀ wọn l'Osun?
Iroyin naa to lu ori ayelujara pa sọ pe ni ṣe lawọn ọlọpaa sa awọn ọdọ kaakiri lawọn oju popo kan niluu Eko ti wọn si fi ọkọ akero nla ko wọn pada si ipinlẹ Osun.


Aminat, akẹ́kọ̀ọ́ táwọn ọlọ́pàá yin tajútajú fọ́ lójú ṣàlàyé bí ọlọ́pàá ṣe jáa jù sílẹ̀ nílé ìwòsàn
Amina ni awọn ọlọpaa naa, ti wọn wa lati agọ ọlọpaa to wa ni agbegbe Dọpẹmu, gbe oun lọ si agọ wọn.


Ọmọọba Harry àti Meghan Markle fẹ́ ṣàbẹ̀wò sí Naijiria l’oṣu karun-un
Invictus Games ni idije ere idaraya ti wọn ṣagbekalẹ rẹ fawọn oṣiṣẹ ologun ati agbofinro ti wọn farapa loju ogun, lati maa fi dun wọn ninu.


Ìjọba fáwọn olùgbé ilé àkọ́patì Ikoyi Tower l'Eko lọ́jọ́ méjì láti kúrò níbẹ̀, bí bẹ́ẹ̀ kọ̀ọ́...
Kọmiṣọna fọrọ eto ayika ati ọrọ omi nipinlẹ naa, Tokunbọ Wahab lo sọ eyi di mimọ lasiko to ṣe abẹwo si agbegbe naa, nibi ti awọn eeyan n sun si lai gba aṣẹ.


Wo bí àṣírí ọ̀gá bánkì tó rí ẹ̀wọn ọdún mọ́kànlélọ́gọ́fà he lórí ẹ̀sùn jìbìtì N112m ṣe tú
Adajọ S. N. Odili gbe idajọ naa kalẹ lẹyin to ni awọn ẹri toun ri gba lori ẹsun ti wọn fi kan Placidus kọja ohun ti wọn le dawọ bo mọlẹ.


Akẹ́kọ̀ọ́ Kwara méjì fakọyọ nínú ìdánwò JAMB, gba máàkì 358 àti 362
Akekọọ ile ẹkọ girama ipinlẹ Kwara wa lara awọn akẹkọọ to fakọyọ julọ ninu idanwo JAMB ọdun 2024.


Àwọn ọ̀dọ́ bẹ̀rẹ̀ ìfẹ̀hónúhàn l’Osun lórí ọ̀wọ́ngógó epo, iná mọ̀nàmọ́ná àti oúnjẹ
Iwọde naa lo waye niluu Osogbo nipinlẹ Osun.


Agbẹjọ́rò wọ́ Adelabu àtàwọn míì lọ sílé ẹjọ́ fẹ́sùn pínpín iná mọ̀nàmọ́ná sí ìsọ́rí
Àwọn mìíràn tí Akingbolu tún pé lẹ́jọ́ ni àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ iná mọ̀nàmọ́ná Nàìjíríà, Nigeria Electricity Regulatory Commission (NERC) àti Ikeja Electricity Distribution Company (IKEDC).


Wọ́n fẹ̀sùn kan Israel pé wọ́n ń pète ogun nípa ìṣekúpa ọmọdé
Ninu iwadi sini ikọ ologun Israel ni West Bank, BBC ṣe afihan ohun to waye lọjọ ti awọn ọmọdekunrin meji naa ku.


Ìjọba Nàíjíríà sọ̀rọ̀ lórí ikú Daniel Anjọrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá tí wọ́n gún pa ní London
Yatọ si eyi, Hainault tun wa lara awọn agbegbe ti awọn eeyan n wa julọ lori ikanni ayelujara ti Google lasiko yii.


Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tún ṣàwárí abẹ́ afárá ni Osborne ní Island tí àwọn èèyàn n gbé
Tokunbọ Wahab ni abẹ afara Osborne to wa ni Ikoyi lawọn ti ṣawari ibi ti awọn eeyan naa sọ di ile wọn lati maa gbe.


Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ fún ìjọba di ìparí oṣù yìí láti san N615,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ tí wọ́n ń bèèrè
Gomina ipinle Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sọ pe ijọba oun ṣetan lati san owo oṣiṣẹ to kere julọ ti ijọba apapọ ba kede.


Àwọn afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn pa èèyàn kan, jó ilé ìgbé méjì gbúrúgbúrú ní Kwara
Iroyin ni lalẹ ọjọ Aje, ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹrin, ọdun 2024 ni rogbodiyan bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa ti wọn si faa titi di ọjọ Iṣẹgun.


Ìjà parí! Ogogo àti Yinka Quadri dìmọ́ ara wọn lẹ́yìn tí Ajobiewe báwọn dá si
Ṣáájú ni àwọn ìròyìn kan ti ń lọ lórí ayélujára pé nǹkan kò lọ déédé láàárín àwọn àgbà òṣèré méjéèjì láti ọdún tó kọjá àmọ́ ọ̀pọ̀ ènìyàn ni kò gbàgbọ́.


Sola Sobowale ṣàlàyé bí ó ṣe rìn ìrìnàjo láti ayé 'Toyin Tomato' lọ ṣé 'Caregiver' ni London
Ilumọka oṣere, ẹni ọdun mejidinlọgọta tan imọlẹ si awọn iṣẹlẹ yii lasiko to n ṣe ifọrọwerọ lori eto Teju Baby Face lọjọ Isẹgun.


Iléeṣẹ́ O Pay ti dá a padà fún CBN, wọ́n si bá àwon Oníbàárà wọn sọ̀rọ̀ pé...
Àwọn ilé iṣẹ́ bíi Opay, Kuda Bank, Palmpay àti Moniepoint ni ọ̀rọ̀ náà kàn, tí wọn kò ní ní àǹfàní láti gba àwọn oníbàárà tuntun láàyè láti ṣí akoto owó pẹ̀lú wọn fún ìgbà kan ná.


A ó fòfin dé 'Loan App' tó bá ń dún kookò mọ́ àwọn onîbàárà wọn- FCCPC
Ọga fun ileeṣẹ ijọba, Federal Competitiona & Consumer Protection Commission, FCCPC ni idunkoko yoo di ohun igbagbe laipẹ.


Kí ló fa gbas-gbos láàrin Davido àti Wizkid lórí ayélujára?
Ori itakun ayelujara X ni rogbodiyan naa ti waye lopin ọsẹ.


Wo ohun tí àwọn aráàlú ń là kọjá nítorí àìrí epo bẹntiróòlù rà lónìí
Bo tilẹ jẹ pe ajọ NNPCL to n ri si ọrọ epo rọbi sọ lopin ọsẹ wi pe awọn ni epo to to ọmọ Naijiria lo ni ipamọ, alukoro ẹgbẹ IPMAN, Ọgbẹni Chinedu Ukadike ti fidi rẹ mulẹ pe ko si epo to to araalu lo ni Naijiria lọwọ yii.


Wo àwọn nǹkan méje tí o kò mọ̀ nípa Egbin Orun, akọrin ẹ̀mí tó dolóògbé
Olorin ẹmi bii tiẹ, Esther Igbẹkẹle, lo fi iroyin iku naa soju opo Instagram rẹ lọjọ Satide, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin yii.


'Ìbejì ni wá ṣùgbọ́n àyẹ̀wò DNA ní bàbá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ló bí wa'
Awọn onimọ sayensi ṣalaye pe, iru iṣẹlẹ yii ṣọwọn, ti ko si ju mẹwa lọ to ni akọsilẹ lagbaye ṣugbọn o wọpọ laarin ẹranko.


Oyún oṣù méje ààbọ̀, tí Dókítà gbé jáde nínú ìyá rẹ̀ ní Gaza, ti jáde láyé
Ẹlẹmi gba ẹmi ọmọ jojolo naa ni Ọjọbọ ana, ti wọn si ti sin i si ẹgbẹ iya rẹ ẹni ti wọn fi orukọ rẹ sọ ọ.


Ìwọ́de gbòde ní Australia láti fòpin sí pípa àwọn obìnrin lọ́nà àìtọ́
Olóòtú ìjọba Australia, Anthony Albanese ní ọ̀rọ̀ náà ti di ohun tó ń dààmú gbogbo orílẹ̀ èdè àwọn.


Kí ló dé tí àwọn èèyàn kan ń fi apá jánú lórí ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Ọ̀yọ́?
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) n'ipinlẹ Ọyọ ti fi ọrọ lede wi pe irọ lasan ni pe eto idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ,


One Step At A Time

This old adage, more relevant than ever



Our Objective

  • Support and encourage current members as and when the need arises fairly and honestly
  • Grow our membership by reaching out through formal and informal social gatherings
  • Extend charitable assistance to the needy and wanting
  • Promote and maintain friendship, members and other colleagues who are non members of Soyuznikis-UK
  • Promote the group locally and worldwide
Our Mission
Soyuznikis-UK is a union for Nigerians who have studied in the former Union of Soviets Socialist Republic (USSR). Soyuznikis comes from the Russian word ‘Soyuz’ meaning union. The association was founded in the summer of 2007 during the wedding ceremony of a colleague in London, the idea came about to form an umbrella organisation to bring together and embrace in friendship as it existed amongst us during our stay in the USSR was agreed.

Soyuznikis-UK is a secular and non political organisation. Membership to the group is not dependent on creed, origin, gender or sexuality. We endeavour to be a progressive organisation that will make meaningful contributions to the communities that gave us the opportunity to learn – USSR, the one that now host us - United Kingdom and most especially our nation – Nigeria. The deeds and acts of Soyuznikis-UK are guided by its constitution.

Our general meetings are held on the last Saturday of every month excluding December, when we normally hold our End of Year Party. Ideally, we as a group encourage our friends and familities to join us on our social events as a way of fostering our interpersonal relationships.

Unity Is Strength

Since inception, the association has been lead by the following persons as President. They have made efforts to foster growth and unity among members.

They are:
  1. Mr. Paul Eboh 2007 to 2009
  2. Dr. Ralph Eke 2009 to 2011
  3. Pastor Chioma Ejiofor 2011 to 2012
  4. Mr. Ebenezer Hundeyin 2012 to 2019
  5. Mr. Olushina Alaka 2019 to date


Cancel Culture - Very Divisive

The most dangerous of all falsehoods is slightly distorted truth. The danger of instant judgements and monolithic narratives are all too prevalent in these deliberations. Where you will find cold-blooded grasping; massive sense of entitlement; an inability to show gratitude; an unrealistic expectation of puritanism from others; and a passionate performance of virtue that is well executed in the public space ( social media) but not in the intimate space of co-habitation and friendship.

These are very trying times. Technology as recent as couple of years ago was supposed to bring us all closer - remember the global village?. The emergence of an old doctrine - critical race theory the epitome of this dramatic change in attitude towards anyone with a different point of view has put paid to that paradigm. These contrive and concerted attack on one race as being the source of the biblical original sin is trivial and false period.

We insulate ourselves in ideological bubbles of similar-thinking people and refuse to countenance or even engage with the truth. We now seems to be building echo chambers with titanium and carbon fibre cladding just to make sure we do not see or hear anything different. If these cancel culture mentality is being adopted to the pandemic, may be herd immunity would have been achieved by now. We have become communities in a dislocated social fabric that is fracturing at an astonishing rate. If we do not amend this fast, rupture seems to be the only ramification.